Saturday
“Ayọ̀ púpọ̀ wà nínú fífúnni ju èyí tó wà nínú rírígbà lọ”—Ìṣe 20:35
Àárọ̀
9:20 Fídíò Orin
9:30 Orin 111 àti Àdúrà
9:40 ‘Ó La Ẹnu Rẹ̀, Ó sì Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Kọ́ Wọn’ (Mátíù 5:1, 2)
9:50 FÍDÍÒ ÌTÀN BÍBÉLÌ:
Ìhìn Rere Látọ̀dọ̀ Jésù: Abala 5
“Bó Ṣe Ń Kọ́ni Lẹ́kọ̀ọ́ Yà Wọ́n Lẹ́nu” (Mátíù 5:3–7:29; Lúùkù 6:17-49)
10:25 Orin 89 àti Ìfilọ̀
10:35 Àwọn Nǹkan Wo Ni Kì Í Jẹ́ Kéèyàn Láyọ̀? (Lúùkù 6:24-26)
10:50 Ṣé O Máa Ń Fòye Mọ Ìlànà Tó Wà Nínú Òfin? (Mátíù 5:17-48)
11:15 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Ohun Tá A Kọ́ Nípa Ibi tí Jésù Dé
• Iyọ̀ àti Ìmọ́lẹ̀ (Mátíù 5:13-16)
• Ewéko àti Ẹranko (Jẹ́nẹ́sísì 1:28, 29; Mátíù 6:19, 26, 28; 7:6, 10, 15, 16)
11:40 ÌRÌBỌMI: ‘Baba Rẹ Tó Ń Rí Ohun Tó Wà ní Ìkọ̀kọ̀ Máa San Ọ́ Lẹ́san’ (Mátíù 6:6)
12:10 Orin 51 àti Àkókò Ìsinmi
Ọ̀sán
1:35 Fídíò Orin
1:45 Orin 125
1:50 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: “Aláyọ̀ Ni . . . ”
• “Àwọn Tó Ń Wá Ìtọ́sọ́nà Ọlọ́run” (Mátíù 5:3)
• “Àwọn Tó Ń Ṣọ̀fọ̀” (Mátíù 5:4)
• “Àwọn Oníwà Tútù” (Mátíù 5:5)
• “Àwọn Tí Ebi Òdodo Ń Pa, Tí Òùngbẹ Òdodo sì Ń Gbẹ” (Mátíù 5:6)
• “Àwọn Aláàánú” (Mátíù 5:7)
• “Àwọn Tí Ọkàn Wọn Mọ́” (Mátíù 5:8)
• “Àwọn Tó Ń Wá Àlàáfíà” (Mátíù 5:9)
• “Àwọn Tí Wọ́n Ṣe Inúnibíni Sí Nítorí Òdodo” (Mátíù 5:10)
• “Yín Tí Àwọn Èèyàn Bá Pẹ̀gàn Yín” (Mátíù 5:11, 12)
3:20 Orin 81 àti Ìfilọ̀
3:30 “Kí Ló Dé Tí Ẹ̀ Ń Ṣàníyàn?” (Mátíù 6:19-33)
3:55 “Ẹ Gba Ẹnubodè Tóóró Wọlé” (Mátíù 7:1-5, 12-14, 16-18, 24-27)
4:30 Orin 21 àti Àdúrà Ìparí