ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 1342-1343
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Máàkù

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Máàkù
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Mátíù
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Lúùkù
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jòhánù
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • A7-E Àwọn Ìṣẹ̀lẹ̀ Pàtàkì Nínú Ìgbésí Ayé Jésù—Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Tó Ta Yọ Tí Jésù Ṣe ní Gálílì (Apá Kejì)
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Máàkù

MÁÀKÙ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Jòhánù Onírìbọmi ń wàásù (1-8)

    • Jésù ṣèrìbọmi (9-11)

    • Sátánì dán Jésù wò (12, 13)

    • Jésù bẹ̀rẹ̀ sí í wàásù ní Gálílì (14, 15)

    • Ó pe àwọn tó kọ́kọ́ di ọmọ ẹ̀yìn (16-20)

    • Ó lé ẹ̀mí àìmọ́ jáde (21-28)

    • Jésù wo ọ̀pọ̀ èèyàn sàn ní Kápánáúmù (29-34)

    • Ó gbàdúrà níbi tó dá (35-39)

    • Ó wo adẹ́tẹ̀ sàn (40-45)

  • 2

    • Jésù wo alárùn rọpárọsẹ̀ sàn (1-12)

    • Jésù pe Léfì (13-17)

    • Wọ́n béèrè nípa ààwẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀ (18-22)

    • Jésù ni “Olúwa Sábáàtì” (23-28)

  • 3

    • Ó wo ọkùnrin tí ọwọ́ rẹ̀ rọ sàn (1-6)

    • Èrò rẹpẹtẹ wá sí èbúté (7-12)

    • Àwọn àpọ́sítélì méjìlá (13-19)

    • Ọ̀rọ̀ òdì sí ẹ̀mí mímọ́ (20-30)

    • Ìyá Jésù àti àwọn arákùnrin rẹ̀ (31-35)

  • 4

    • ÀWỌN ÀPÉJÚWE NÍPA ÌJỌBA NÁÀ (1-34)

      • Afúnrúgbìn (1-9)

      • Ìdí tí Jésù fi lo àwọn àpèjúwe (10-12)

      • Ó ṣàlàyé ìtumọ̀ àpèjúwe afúnrúgbìn (13-20)

      • A kì í gbé fìtílà sábẹ́ apẹ̀rẹ̀ (21-23)

      • Òṣùwọ̀n tí ẹ fi ń díwọ̀n (24, 25)

      • Afúnrúgbìn tó sùn (26-29)

      • Hóró músítádì (30-32)

      • Ó ń lo àpèjúwe (33, 34)

    • Jésù mú kí ìjì dáwọ́ dúró (35-41)

  • 5

    • Jésù lé àwọn ẹ̀mí èṣù lọ sínú ẹlẹ́dẹ̀ (1-20)

    • Ọmọbìnrin Jáírù; obìnrin kan fọwọ́ kan aṣọ àwọ̀lékè Jésù (21-43)

  • 6

    • Wọn ò tẹ́wọ́ gba Jésù ní ìlú rẹ̀ (1-6)

    • Ó fún àwọn Méjìlá náà ní ìtọ́ni nípa iṣẹ́ ìwàásù (7-13)

    • Wọ́n pa Jòhánù Onírìbọmi (14-29)

    • Jésù bọ́ 5,000 èèyàn (30-44)

    • Jésù rìn lórí omi (45-52)

    • Ó ṣe ìwòsàn ní Jẹ́nẹ́sárẹ́tì (53-56)

  • 7

    • Ó tú àṣírí àwọn àṣà àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn èèyàn (1-13)

    • Inú ọkàn ni ohun tó ń sọni di aláìmọ́ ti ń wá (14-23)

    • Ìgbàgbọ́ obìnrin tó jẹ́ ọmọ ilẹ̀ Foníṣíà ní Síríà (24-30)

    • Ó wo adití sàn (31-37)

  • 8

    • Jésù bọ́ 4,000 èèyàn (1-9)

    • Wọ́n béèrè àmì (10-13)

    • Ìwúkàrà àwọn Farisí àti ti Hẹ́rọ́dù (14-21)

    • Ó wo afọ́jú kan sàn ní Bẹtisáídà (22-26)

    • Pétérù pè é ní Kristi (27-30)

    • Àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikú Jésù (31-33)

    • Ojúlówó ọmọ ẹ̀yìn (34-38)

  • 9

    • A yí Jésù pa dà di ológo (1-13)

    • Ó wo ọmọkùnrin tí ẹ̀mí èṣù ń yọ lẹ́nu sàn (14-29)

      • Ohun gbogbo ṣeé ṣe fún ẹni tó ní ìgbàgbọ́ (23)

    • Jésù tún sọ tẹ́lẹ̀ nípa ikú rẹ̀ (30-32)

    • Àwọn ọmọ ẹ̀yìn ń jiyàn nípa ẹni tó tóbi jù (33-37)

    • Ẹni tí kò bá ta kò wá, tiwa ló ń ṣe (38-41)

    • Àwọn ohun ìkọ̀sẹ̀ (42-48)

    • “Ẹ ní iyọ̀ nínú ara yín” (49, 50)

  • 10

    • Ìgbéyàwó àti ìkọ̀sílẹ̀ (1-12)

    • Jésù súre fún àwọn ọmọdé (13-16)

    • Ìbéèrè ọkùnrin ọlọ́rọ̀ (17-25)

    • Àwọn ohun tí a yááfì torí Ìjọba náà (26-31)

    • Jésù tún sọ tẹ́lẹ̀ nípa ikú rẹ̀ (32-34)

    • Ohun tí Jémíìsì àti Jòhánù béèrè (35-45)

      • Jésù fi ẹ̀mí rẹ̀ ṣe ìràpadà fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn (45)

    • Ó wo Báátíméù afọ́jú sàn (46-52)

  • 11

    • Jésù gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọnú ìlú (1-11)

    • Ó gégùn-ún fún igi ọ̀pọ̀tọ́ (12-14)

    • Jésù fọ tẹ́ńpìlì mọ́ (15-18)

    • Ohun tí a rí kọ́ lára igi ọ̀pọ̀tọ́ tó rọ (19-26)

    • Wọ́n béèrè ẹni tó fún Jésù ní àṣẹ (27-33)

  • 12

    • Àpèjúwe àwọn tó ń dáko tí wọ́n sì pààyàn (1-12)

    • Ọlọ́run àti Késárì (13-17)

    • Ìbéèrè nípa àjíǹde (18-27)

    • Àṣẹ méjì tó tóbi jù (28-34)

    • Ṣé ọmọ Dáfídì ni Kristi? (35-37a)

    • Ó ní kí wọ́n ṣọ́ra fún àwọn akọ̀wé òfin (37b-40)

    • Opó aláìní fi ẹyọ owó méjì sílẹ̀ (41-44)

  • 13

    • ÌPARÍ ÈTÒ ÀWỌN NǸKAN (1-37)

      • Ogun, ìmìtìtì ilẹ̀, àìtó oúnjẹ (8)

      • A máa wàásù ìhìn rere (10)

      • Ìpọ́njú ńlá (19)

      • Ọmọ èèyàn ń bọ̀ (26)

      • Àpèjúwe igi ọ̀pọ̀tọ́ (28-31)

      • Ẹ máa ṣọ́nà (32-37)

  • 14

    • Àwọn àlùfáà gbìmọ̀ pọ̀ láti pa Jésù (1, 2)

    • Ó da òróró onílọ́fínńdà sórí Jésù (3-9)

    • Júdásì da Jésù (10, 11)

    • Ìrékọjá tó gbẹ̀yìn (12-21)

    • Jésù fi Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa lọ́lẹ̀ (22-26)

    • Ó sọ tẹ́lẹ̀ pé Pétérù máa sẹ́ òun (27-31)

    • Jésù gbàdúrà ní Gẹ́tísémánì (32-42)

    • Wọ́n mú Jésù (43-52)

    • Wọ́n gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ níwájú Sàhẹ́ndìrìn (53-65)

    • Pétérù sẹ́ Jésù (66-72)

  • 15

    • Jésù dé iwájú Pílátù (1-15)

    • Wọ́n fi ṣẹlẹ́yà ní gbangba (16-20)

    • Wọ́n kàn án mọ́gi ní Gọ́gọ́tà (21-32)

    • Ikú Jésù (33-41)

    • Wọ́n sìnkú Jésù (42-47)

  • 16

    • Jésù jíǹde (1-8)

    Yorùbá Publications (1987-2026)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2026 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́