December 5-11
2 ÀWỌN ỌBA 13-15
Orin 127 àti Àdúrà
Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)
ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN
“Jèhófà Máa Ń Bù Kún Ìsapá Tá A Bá Fi Gbogbo Ọ̀kan Ṣe”: (10 min.)
Àwọn Ẹ̀kọ́ Iyebíye Míì: (10 min.)
2Ọb 13:20, 21—Ṣé iṣẹ́ ìyanu yìí fi hàn pé ó dáa kéèyàn máa jọ́sìn àwọn tó ti kú? (w05 8/1 11 ¶3)
Àwọn ẹ̀kọ́ iyebíye wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì?
Bíbélì Kíkà: (4 min.) 2Ọb 13:20–14:7 (th ẹ̀kọ́ 10)
TẸRA MỌ́ IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ
Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min.) Àkòrí ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ ni kó o fi bẹ̀rẹ̀. Fún ẹni náà ní ìwé Gbádùn Ayé Rẹ Títí Láé!—Ìbẹ̀rẹ̀ Ẹ̀kọ́ Bíbélì. (th ẹ̀kọ́ 1)
Ìpadàbẹ̀wò: (5 min.) Bẹ̀rẹ̀ ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì ní ẹ̀kọ́ 01 ìwé Gbádùn Ayé Rẹ Títí Láé!—Ìbẹ̀rẹ̀ Ẹ̀kọ́ Bíbélì. (th ẹ̀kọ́ 20)
Àsọyé: (5 min.) km 8/03 7—Àkòrí: Iṣẹ́ Tó Ń Tuni Lára. (th ẹ̀kọ́ 11)
MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI
“Jèhófà Ò Ní Gbàgbé Iṣẹ́ Wa”: (10 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò Jèhófà Kò Ní Gbàgbé.
Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ: (5 min.)
Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) lff ẹ̀kọ́ 30
Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min.)
Orin 151 àti Àdúrà